1Ìyìn ń dúró dè ọ́, Ọlọ́run, ní Sioni;
2Ìwọ tí ó ń gbọ́ àdúrà,
3Ọ̀ràn àìṣedéédéé borí mi bí ó ṣe ti ìrékọjá wa ni!
4Ìbùkún ni fún àwọn tí o yàn
5Ìwọ dá wa lóhùn pẹ̀lú ohun ìyanu ti òdodo,
6ìwọ tí ó dá òkè nípa agbára rẹ,
7ẹni tí ó mú rírú omi òkun dákẹ́,
8Àwọn tí ó ń gbé òkèrè bẹ̀rù,
9Ìwọ bẹ ayé wò, o sì bomirin;
10Ìwọ fi bomirin sí aporo rẹ̀
11Ìwọ fi oore rẹ dé ọdún ní adé,
12Pápá tútù ní aginjù ń kan
13Agbo ẹran ni a fi wọ pápá tútù náà ní aṣọ;