1Gbóhùn mi, Ọlọ́run, bí mo ti ń sọ àròyé mi
2Pa mí mọ́ kúrò lọ́wọ́ ìmọ̀ ìkọ̀kọ̀ àwọn ènìyàn búburú
3Wọ́n pọ́n ahọ́n wọn bí idà,
4Wọ́n tafà ní ìkọ̀kọ̀ sí àwọn aláìlẹ́ṣẹ̀:
5Wọ́n, gba ara wọn níyànjú nínú èrò búburú,
6Wọ́n gbìmọ̀ àìṣòdodo, wọ́n wí pé,
7Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò ta wọ́n ní ọfà;
8Ahọ́n wọn yóò sì dojú ìjà kọ wọ́n, yóò sì run wọ́n,
9Gbogbo ènìyàn yóò máa bẹ̀rù
10Jẹ́ kí olódodo kí ó yọ̀ nínú Olúwa