1Èmi yóò gbé ojú mi sórí òkè wọ̀n-ọn-nì—
2Ìrànlọ́wọ́ mi tí ọwọ́ Olúwa wá,
3Òun kì yóò jẹ́ kí ẹsẹ̀ rẹ kí ó yẹ̀;
4Kíyèsi, ẹni tí ń pa Israẹli mọ́,
5Olúwa ni olùpamọ́ rẹ;
6Oòrùn kì yóò pa ọ́ ní ìgbà ọ̀sán
7Olúwa yóò pa ọ́ mọ́ kúrò nínú ibi gbogbo
8Olúwa yóò pa àlọ àti ààbọ̀ rẹ mọ́