1Inú mi dùn nígbà tí wọ́n wí fún mi pé,
2Ẹsẹ̀ wa yóò dúró ní ẹnu ibodè rẹ,
3Jerusalẹmu, ìwọ tí a kọ́ bí ìlú
4Níbi tí àwọn ẹ̀yà máa ń gòkè lọ,
5Nítorí ibẹ̀ ni a gbé ìtẹ́ ìdájọ́ kalẹ̀,
6Gbàdúrà fún àlàáfíà Jerusalẹmu;
7Kí àlàáfíà kí ó wà nínú odi rẹ̀,
8Nítorí àwọn ọkùnrin àti àwọn ẹgbẹ́ mi
9Nítorí ilé Olúwa Ọlọ́run wa,