1Èmi ké pe Olúwa nínú ìpọ́njú mi,
2Gbà mí, Olúwa, kúrò lọ́wọ́ ètè èké
3Kí ni kí a fi fún ọ?
4Òun yóò bá ọ wí pẹ̀lú ọfà mímú ológun,
5Ègbé ni fún mi tí èmi ṣe àtìpó ní Meṣeki,
6Ó ti pẹ́ tí èmi ti ń gbé
7Ènìyàn àlàáfíà ni mí;
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá
1Èmi ké pe Olúwa nínú ìpọ́njú mi,
2Gbà mí, Olúwa, kúrò lọ́wọ́ ètè èké
3Kí ni kí a fi fún ọ?
4Òun yóò bá ọ wí pẹ̀lú ọfà mímú ológun,
5Ègbé ni fún mi tí èmi ṣe àtìpó ní Meṣeki,
6Ó ti pẹ́ tí èmi ti ń gbé
7Ènìyàn àlàáfíà ni mí;