1Ẹni tí ó sì ń ṣorí kunkun lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìbáwí
2Nígbà tí olódodo bá ń gbilẹ̀, àwọn ènìyàn a yọ̀
3Ènìyàn tí ó fẹ́ràn ọgbọ́n mú kí baba rẹ̀ láyọ̀
4Nípa ìdájọ́ òdodo ni ọba fi í mú ìlú tòrò nini,
5Ẹnikẹ́ni tí ó bá tan aládùúgbò rẹ̀
6Ẹ̀ṣẹ̀ ènìyàn ibi ni ó jẹ́ ìdẹ̀kùn rẹ̀
7Olódodo ń máa ro ọ̀rọ̀ tálákà,
8Àwọn ẹlẹ́yà a máa ru ìlú sókè,
9Bí ọlọ́gbọ́n ènìyàn bá lọ sí ilé ẹjọ́ pẹ̀lú aláìgbọ́n
10Àwọn tí ó ń tàjẹ̀ sílẹ̀ kò rí ẹni dídúró ṣinṣin
11Aláìgbọ́n ènìyàn fi gbogbo ẹnu rẹ̀ bínú
12Bí olórí bá fetí sí irọ́,
13Tálákà ènìyàn àti aninilára jọ ní àbùdá yìí,
14Bí ọba kan bá ń ṣe ìdájọ́ tálákà pẹ̀lú òtítọ́
15Ọ̀pá ìbániwí ń fún ni ní ọgbọ́n
16Nígbà tí ènìyàn búburú ń gbilẹ̀, bẹ́ẹ̀ náà ni ẹ̀ṣẹ̀ ń gbilẹ̀
17Bá ọmọ rẹ wí, yóò sì fún ọ ní àlàáfíà
18Níbi tí kò ti sí ìfihàn, àwọn ènìyàn a gbé ìgbé ayé àìbìkítà,
19A kò le fi ọ̀rọ̀ lásán kìlọ̀ fún ìránṣẹ́
20Ǹjẹ́ ó rí ènìyàn tí ń kánjú sọ̀rọ̀?
21Bí ènìyàn kan bá kẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ lákẹ̀ẹ́jù láti kékeré
22Oníbìínú ènìyàn a ru ìjà sókè,
23Ìgbéraga ènìyàn a máa sọ ọ́ di ẹni ilẹ̀
24Ẹni tí ó ń kó ẹgbẹ́, olè kórìíra ọkàn ara rẹ̀,
25Ìbẹ̀rù ènìyàn kan yóò sì di ìdẹ̀kùn
26Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ń wá ojúrere alákòóso,
27Olódodo kórìíra àwọn aláìṣòótọ́: