1Ènìyàn búburú ń sá bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹnìkan kò lé e
2Nígbà tí orílẹ̀-èdè bá ní orí kunkun, àwọn ọba rẹ̀ a máa pọ̀,
3Ọba tí ó ni àwọn tálákà lára
4Àwọn tí ó kọ òfin sílẹ̀ a máa gbóríyìn fún ènìyàn búburú
5Òye ìdájọ́ òdodo kò yé àwọn ẹni ibi
6Ó sàn láti jẹ́ tálákà tí ìrìn rẹ̀ jẹ́ aláìlábùkù
7Ẹni tí ó pa òfin mọ́ jẹ́ olóye ọmọ
8Ẹni tí ó mú ọrọ̀ rẹ̀ di púpọ̀ nípa èrè àjẹjù
9Bí ẹnikẹ́ni bá kọ etí ikún sí òfin,
10Ẹni tí ó mú olódodo rìn ọ̀nà búburú
11Ọlọ́rọ̀ ènìyàn le è gbọ́n lójú ara rẹ̀
12Nígbà tí olódodo ń lékè ariwo ayọ̀ ta;
13Ẹni tí ó bo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ kì yóò ṣe rere,
14Ìbùkún ni fún ènìyàn náà tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run nígbà gbogbo
15Bí kìnnìún tí ń ké tàbí Beari tí ń halẹ̀
16Ọmọ-aládé tí ó ṣe aláìmòye púpọ̀ ní ń ṣe ìwà ìkà púpọ̀ pẹ̀lú,
17Ẹni tí ọkàn rẹ̀ kò balẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ìpànìyàn
18Ẹni tí ń rìn déédéé ní yóò là,
19Ẹni tí ó bá ro ilẹ̀ rẹ̀ yóò ní oúnjẹ lọ́pọ̀lọ́pọ̀
20Olóòtítọ́ ènìyàn yóò rí ìbùkún gbà gan an
21Ojúsàájú ṣíṣe kò dára,
22Ahun ń sáré àti là
23Ẹni tí ó bá ènìyàn kan wí yóò rí ojúrere ni nígbẹ̀yìn
24Ẹni tí ó ja baba tàbí ìyá rẹ̀ lólè
25Ọ̀kánjúwà ènìyàn a máa dá ìjà sílẹ̀,
26Ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀lé ara rẹ̀ jẹ́ aláìgbọ́n
27Ẹni tí ó ń fi fún tálákà kì yóò ṣe aláìní ohunkóhun,
28Nígbà tí ènìyàn búburú bá dórí ìjọba, àwọn ènìyàn a na pápá bora;