1Má ṣe yangàn nítorí ọ̀la
2Jẹ́ kí ẹlòmíràn yìn ọ́ dípò ẹnu ara rẹ,
3Òkúta wúwo, erùpẹ̀ sì wúwo
4Ìbínú ni ìkà, ìrunú sì burú púpọ̀
5Ìbániwí gbangba sàn
6Òtítọ́ ni ọgbẹ́ ọ̀rẹ́,
7Kódà oyin kò dùn lẹ́nu ẹni tí ó ti yó
8Bí ẹyẹ tí ó ṣáko lọ kúrò níbi ìtẹ́ rẹ̀
9Ìpara olóòórùn dídùn àti tùràrí ń mú ayọ̀ wá sínú ọkàn
10Má ṣe kọ ọ̀rẹ́ rẹ àti ọ̀rẹ́ baba rẹ sílẹ̀,
11Gbọ́n, ọmọ mi, kí o sì mú ayọ̀ wá sínú ọkàn mi
12Ọlọ́gbọ́n rí ewu, ó sì fi ara pamọ́
13Gba aṣọ ẹni tí ó ṣe onídùúró fún àjèjì
14Bí ènìyàn kan ń kígbe súre fún aládùúgbò rẹ ní òwúrọ̀
15Àyà tí ó máa ń jà dàbí
16dídá a lẹ́kun dàbí ìgbà tí ènìyàn ń dá afẹ́fẹ́ lẹ́kun
17Bí irin tí ń pọ́n irin mú
18Ẹni tí ó tọ́jú igi ọ̀pọ̀tọ́ yóò jẹ èso rẹ̀
19Bí omi tí ń ṣe àfihàn ojú, nígbà tí a bá wò ó
20Kò tẹ́ ikú àti ìparun lọ́rùn rí
21Iná fún fàdákà iná ìléru fún wúrà,
22Bí a tilẹ̀ gún aláìgbọ́n nínú odó,
23Rí i dájú pé o mọ ipò tí àwọn agbo àgùntàn rẹ wà
24nítorí ọrọ̀ kì í pẹ́ lọ títí
25Nígbà tí a bá kó koríko, ewéko tuntun yóò sì hù jáde, a ó sì kó koríko àwọn orí òkè wọlé
26àwọn àgùntàn yóò pèsè aṣọ fún ọ,
27Ìwọ yóò ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ wàrà ewúrẹ́