1Àwọn ọ̀rọ̀ Aguri ọmọ Jake, ọ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ tí ọkùnrin yìí sọ fún Itieli.
2“Èmi ni aláìmòye ju nínú àwọn ènìyàn;
3Èmi kò tilẹ̀ kọ́ ọgbọ́n
4Ta ni ó ti gòkè lọ sí ọ̀run tí ó sì padà sọ̀kalẹ̀?
5“Gbogbo ọ̀rọ̀ Ọlọ́run jẹ́ aláìlábùkù;
6Má ṣe fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀,
7“Ohun méjì ni mo ń béèrè lọ́wọ́ rẹ, Olúwa;
8Mú èké ṣíṣe àti irọ́ jìnnà sí mi;
9Àìṣe bẹ́ẹ̀, mo lè ní àníjù kí n sì gbàgbé rẹ
10“Má ṣe ba ìránṣẹ́ lórúkọ jẹ́ lọ́dọ̀ ọ̀gá rẹ̀,
11“Àwọn kan wá ṣépè fún àwọn baba wọn
12Àwọn tí ó mọ́ ní ojú ara wọn
13àwọn ẹni tí ojú wọn gbéga nígbà gbogbo,
14Àwọn ẹni tí eyín wọn jẹ́ idà
15“Eṣúṣú ni ọmọbìnrin méjì.
16Ibojì, inú tí ó yàgàn,
17“Ojú tí ń fi baba ṣẹ̀fẹ̀,
18“Àwọn nǹkan mẹ́ta wà tí ó jẹ́ ìyàlẹ́nu fún mi,
19ipa ẹyẹ idì ní òfúrufú
20“Èyí ni ọ̀nà alágbèrè obìnrin
21“Lábẹ́ nǹkan mẹ́ta ni ilé ayé ti ń wárìrì
22Ìránṣẹ́ tí ó di ọba
23obìnrin tí gbogbo ènìyàn kórìíra tí ó sì wá lọ́kọ
24“Àwọn ohun mẹ́rin ló kéré láyé
25Àwọn èèrà jẹ́ aláìlágbára ẹ̀dá,
26Ehoro jẹ́ aláìlágbára ẹ̀dá;
27àwọn eṣú kò ní ọba,
28Ọmọnílé fi ọwọ́ rẹ̀ dì mú,
29“Àwọn ohun mẹ́ta ní ń bẹ tí ń rìn rere,
30Kìnnìún, alágbára láàrín ẹranko tí kì í sá fún ohunkóhun
31Ẹsin tí a dì lẹ́gbẹ̀ẹ́;
32“Bí ìwọ bá ti hùwà aṣiwèrè nípa gbígbé ara rẹ ga,
33Nítorí bí fífún omi ọmú tí í mú wàrà wá,