1Ọkàn ọba ń bẹ lọ́wọ́ Olúwa;
2Gbogbo ọ̀nà ènìyàn dàbí i pé ó dára lójú rẹ̀,
3Ṣíṣe ohun tí ó dára tí ó sì tọ̀nà
4Ojú tí ó gbéga àti ọkàn ìgbéraga,
5Ètè àwọn olóye jásí èrè
6Ìṣúra tí a kójọ nípasẹ̀ ahọ́n tí ń parọ́
7Ìwà ipá àwọn ènìyàn búburú yóò wọ́ wọn lọ,
8Ọ̀nà ẹlẹ́ṣẹ̀ kún fún ìwà ẹ̀ṣẹ̀
9Ó sàn láti máa gbé ní kọ̀rọ̀ orí òrùlé
10Ènìyàn búburú ń fẹ́ ibi
11Nígbà tí a bá ń fìyà jẹ ẹlẹ́gàn,
12Olódodo ṣàkíyèsí ilé ènìyàn búburú
13Ẹnikẹ́ni tí ó bá ti di etí rẹ̀ sí igbe olùpọ́njú,
14Ọ̀rẹ́ ìkọ̀kọ̀, mú ìbínú kúrò:
15Ayọ̀ ni fún olódodo láti ṣe ìdájọ́:
16Ẹni tí ó bá yà kúrò ní ọ̀nà òye,
17Ẹni tí ó bá fẹ́ afẹ́, yóò di tálákà:
18Ènìyàn búburú ni yóò ṣe owó ìràpadà fún olódodo,
19Ó sàn láti jókòó ní aginjù ju pẹ̀lú
20Ìṣúra iyebíye àti òróró wà ní ibùgbé ọlọ́gbọ́n;
21Ẹni tí ó bá tẹ̀lé òdodo àti àánú yóò rí ìyè,
22Ọlọ́gbọ́n gòkè odi ìlú àwọn alágbára,
23Ẹnikẹ́ni tí ó bá pa ẹnu àti ahọ́n rẹ̀ mọ́,
24Agbéraga àti alágídí ènìyàn ń gan orúkọ ara rẹ̀ nítorí ó ń hùwà nínú ìwà ìgbéraga rẹ̀,
25Ẹlẹ́rìí èké yóò ṣègbé, àwọn tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀ yóò parun láé;
26Ó ń fi ìlara ṣe ojúkòkòrò ní gbogbo ọjọ́:
27Ẹbọ ènìyàn búburú, ìríra ni:
28Ẹlẹ́rìí èké yóò ṣègbé:
29Ènìyàn búburú mú ojú ara rẹ̀ le:
30Kò sí ọgbọ́n, kò sí ìmòye,
31A ń múra ẹṣin sílẹ̀ de ọjọ́ ogun: