We Believe JesusFé, Esperança e Nova Vida

Òwe 20

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá

← Òwe 19 Òwe Òwe 21 →

1Ẹlẹ́yà ni ọtí wáìnì, aláriwo sì ní ọtí líle;

2Ìbẹ̀rù ọba dàbí kíké e kìnnìún;

3Iyì ni ó jẹ́ fún ènìyàn láti sá fún ìjà,

4Ọ̀lẹ kì í ṣiṣẹ́ oko nígbà tí ó yẹ,

5Ète ọkàn ènìyàn dàbí omi jíjìn;

6Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni wọ́n máa ń sọ pe àwọn ní ìfẹ́ àìṣẹ̀tàn,

7Olódodo ènìyàn a máa gbé ìgbé ayé àìlábùkù

8Nígbà tí ọba bá jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀ láti ṣe ìdájọ́

9Ta ni ó le è wí pé, “Mo ti ṣe ọkàn mi ní mímọ́,

10Ìwọ̀n èké àti òsùwọ̀n ìrẹ́jẹ

11Kódà a mọ ọmọdé nípa iṣẹ́ rẹ̀

12Etí tí ó ń gbọ́ àti ojú tí ó ń ríran

13Má ṣe fẹ́ràn oorun, àìṣe bẹ́ẹ̀ ìwọ yóò di tálákà.

14“Kò dára, kò dára!” ní ẹni tó ra ọjà máa ń wí;

15Wúrà wà, iyùn sì wà rẹpẹtẹ,

16Gba abọ́ ẹni tí ó ṣe onídùúró fún àlejò;

17Oúnjẹ tí a fi ọ̀nà èrú rí máa ń dùn lẹ́nu ènìyàn,

18Pa ètè rẹ mọ́ nípa wíwá ìmọ̀ràn

19Olófòófó a máa tú àṣírí

20Bí ènìyàn kan bá ṣépè fún baba tàbí ìyá rẹ̀,

21Ogún tí a kójọ kíákíá ní ìbẹ̀rẹ̀

22Má ṣe wí pé, “N ó sẹ̀san àṣìṣe rẹ yìí fún ọ.”

23Olúwa kórìíra òdínwọ̀n èké.

24Olúwa ni ó ń ṣe olùdarí ìgbésẹ̀ ènìyàn.

25Ìdẹ̀kùn ni fún ènìyàn láti ṣe ìlérí kíákíá

26Ọlọ́gbọ́n ọba tú ènìyàn búburú ká;

27Àtùpà Olúwa ń ṣe àwárí ẹ̀mí ènìyàn

28Ìfẹ́ àti òdodo pa ọba mọ́,

29Ògo àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin ni agbára wọn,

30Ìgbájú ìgbámú àti ìfarapa máa ń mú ibi lọ,

← Òwe 19 Òwe Òwe 21 →

Òwe 20 — iorubá:

Biblica® Open Nkanda wu Moyo, Nguizani Yimona ayi Minkunga 2002