1Ẹlẹ́yà ni ọtí wáìnì, aláriwo sì ní ọtí líle;
2Ìbẹ̀rù ọba dàbí kíké e kìnnìún;
3Iyì ni ó jẹ́ fún ènìyàn láti sá fún ìjà,
4Ọ̀lẹ kì í ṣiṣẹ́ oko nígbà tí ó yẹ,
5Ète ọkàn ènìyàn dàbí omi jíjìn;
6Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni wọ́n máa ń sọ pe àwọn ní ìfẹ́ àìṣẹ̀tàn,
7Olódodo ènìyàn a máa gbé ìgbé ayé àìlábùkù
8Nígbà tí ọba bá jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀ láti ṣe ìdájọ́
9Ta ni ó le è wí pé, “Mo ti ṣe ọkàn mi ní mímọ́,
10Ìwọ̀n èké àti òsùwọ̀n ìrẹ́jẹ
11Kódà a mọ ọmọdé nípa iṣẹ́ rẹ̀
12Etí tí ó ń gbọ́ àti ojú tí ó ń ríran
13Má ṣe fẹ́ràn oorun, àìṣe bẹ́ẹ̀ ìwọ yóò di tálákà.
14“Kò dára, kò dára!” ní ẹni tó ra ọjà máa ń wí;
15Wúrà wà, iyùn sì wà rẹpẹtẹ,
16Gba abọ́ ẹni tí ó ṣe onídùúró fún àlejò;
17Oúnjẹ tí a fi ọ̀nà èrú rí máa ń dùn lẹ́nu ènìyàn,
18Pa ètè rẹ mọ́ nípa wíwá ìmọ̀ràn
19Olófòófó a máa tú àṣírí
20Bí ènìyàn kan bá ṣépè fún baba tàbí ìyá rẹ̀,
21Ogún tí a kójọ kíákíá ní ìbẹ̀rẹ̀
22Má ṣe wí pé, “N ó sẹ̀san àṣìṣe rẹ yìí fún ọ.”
23Olúwa kórìíra òdínwọ̀n èké.
24Olúwa ni ó ń ṣe olùdarí ìgbésẹ̀ ènìyàn.
25Ìdẹ̀kùn ni fún ènìyàn láti ṣe ìlérí kíákíá
26Ọlọ́gbọ́n ọba tú ènìyàn búburú ká;
27Àtùpà Olúwa ń ṣe àwárí ẹ̀mí ènìyàn
28Ìfẹ́ àti òdodo pa ọba mọ́,
29Ògo àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin ni agbára wọn,
30Ìgbájú ìgbámú àti ìfarapa máa ń mú ibi lọ,