1Ó sàn kí ènìyàn jẹ́ tálákà tí ìrìn rẹ̀ kò lábùkù
2Kò dára láti ní ìtara láìní ìmọ̀,
3Ìwà òmùgọ̀ ènìyàn fúnra rẹ̀ a pa ẹ̀mí rẹ̀ run;
4Ọrọ̀ máa ń fa ọ̀rẹ́ púpọ̀;
5Ajẹ́rìí èké kò ní lọ láìjìyà,
6Ọ̀pọ̀ ń wá ojúrere olórí;
7Gbogbo ará ilé e tálákà ni ó pa á tì,
8Ẹni tí ó gba ọgbọ́n fẹ́ràn ọkàn ara rẹ̀;
9Ajẹ́rìí èké kì yóò lọ láìjìyà
10Kò yẹ aláìgbọ́n láti máa gbé nínú ọláńlá,
11Ọgbọ́n ènìyàn a máa fún un ní sùúrù;
12Ìbínú ọba dàbí kíké e kìnnìún,
13Aṣiwèrè ọmọ jẹ́ ìparun baba rẹ̀,
14A máa ń jogún ilé àti ọrọ̀ lọ́dọ̀ òbí,
15Ọ̀lẹ ṣíṣe máa ń fa oorun sísùn fọnfọn,
16Ẹnikẹ́ni tí ó gbọ́ ẹ̀kọ́ pa ẹnu rẹ̀ mọ́,
17Ẹni tí ó ṣàánú tálákà, Olúwa ní ó yá,
18Bá ọmọ rẹ wí nítorí nínú ìyẹn ni ìrètí wà;
19Ènìyàn onínú-fùfù gbọdọ̀ gba èrè ìwà rẹ̀;
20Fetí sí ìmọ̀ràn kí o sì gba ẹ̀kọ́,
21Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ète inú ọkàn ènìyàn,
22Ohun tí ènìyàn ń fẹ́ ni ìfẹ́ tí kì í yẹ̀;
23Ìbẹ̀rù Olúwa ń mú ìyè wá;
24Ọ̀lẹ ki ọwọ́ rẹ̀ bọ inú àwo oúnjẹ;
25Na ẹlẹ́gàn, òpè yóò sì kọ́gbọ́n;
26Ẹni tí ó ṣìkà sí baba rẹ̀, tí ó sì lé ìyá rẹ̀ jáde
27Ọmọ mi, dẹ́kun láti tẹ́tí sí ẹ̀kọ́,
28Ẹlẹ́rìí búburú fi ìdájọ́ ṣẹ̀sín,
29A ti pèsè ìjìyà sílẹ̀ fún ẹlẹ́gàn;