1nígbà tí èmi ìbá mú Israẹli láradá.
2ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀ pé
3“Wọ́n ń mú inú ọba dùn pẹ̀lú ìwà búburú wọn,
4Alágbèrè ni gbogbo wọn
5Ní ọjọ́ àjọ̀dún ọba wa
6Ọkàn wọn ń gbóná bí i ààrò
7Gbogbo wọn gbóná bí ààrò
8“Efraimu ti darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn náà;
9Àwọn àlejò ti jẹ agbára rẹ̀ run
10Ìgbéraga Israẹli ń jẹ́rìí sí i
11“Efraimu dàbí àdàbà
12Nígbà tí wọ́n bá lọ, èmi ó ta àwọ̀n mi sórí wọn,
13Ègbé ní fún wọn,
14Wọn kò kégbe pè mí láti ọkàn wọn,
15Mo kọ́ wọn, mo sì fún wọn ní agbára,
16Wọn kò padà sí ọ̀dọ̀ Ọ̀gá-ògo;