1“Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a padà sọ́dọ̀ Olúwa
2Lẹ́yìn ọjọ́ méjì, yóò sọ wá jí
3Ẹ jẹ́ kí a mọ Olúwa;
4“Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Efraimu?
5Nítorí náà ni mo ṣe gé e yín sí wẹ́wẹ́ láti ọwọ́ àwọn wòlíì,
6Nítorí àánú ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ;
7Bí i Adamu, wọ́n da májẹ̀mú
8Gileadi jẹ́ ìlú àwọn ènìyàn búburú
9Bí adigunjalè ṣe ń ba ní bùba de àwọn ènìyàn
10Mo ti rí ohun tó ba ni lẹ́rù
11“Àti fún ìwọ, Juda,