1“Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yìn àlùfáà!
2Àwọn ọlọ̀tẹ̀ ti gbilẹ̀ nínú ìpànìyàn
3mo mọ ohun gbogbo nípa Efraimu
4“Ìṣe wọn kò gbà wọ́n láààyè
5Ìgbéraga Israẹli ń jẹ́rìí lé wọn;
6Nígbà tí wọ́n bá lọ pẹ̀lú agbo ẹran
7Wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Olúwa
8“Fọn fèrè ní Gibeah,
9Efraimu yóò di ahoro
10Àwọn olórí Juda dàbí àwọn tí í
11A ni Efraimu lára,
12Mo dàbí kòkòrò aṣọ sí Efraimu,
13“Nígbà ti Efraimu ri àìsàn rẹ̀,
14Nítorí pé, èmi ó dàbí kìnnìún sí Efraimu,
15Nígbà náà ni èmi ó padà lọ sí ààyè mi