1Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ọmọ Israẹli,
2àfi èpè, irọ́ pípa àti ìpànìyàn
3Nítorí èyí, ilẹ̀ náà ń ṣọ̀fọ̀,
4“Ṣùgbọ́n kí ẹnikẹ́ni má ṣe mú ẹ̀sùn wá,
5Ẹ ń ṣubú lọ́sàn án àti lóru
6àwọn ènìyàn mi ń ṣègbé nítorí pé wọn kò ní ìmọ̀.
7Bí àwọn àlùfáà ṣe ń pọ̀ sí i
8wọ́n ń jẹun nípa ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi,
9Yóò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ṣe rí náà ni àwọn àlùfáà rí.
10“Wọn ó máa jẹun ṣùgbọ́n wọn kò ní yó;
11fún àgbèrè;
12Wọ́n ń gba ìmọ̀ràn lọ́wọ́ ère igi
13Wọ́n ń rú ẹbọ lórí àwọn òkè ńlá,
14“Èmi kò ní jẹ àwọn ọmọbìnrin yín
15“Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o ṣe àgbèrè ìwọ Israẹli,
16Àwọn ọmọ Israẹli ṣe agídí
17Efraimu ti darapọ̀ mọ́
18Bí ohun mímu wọn bá tilẹ̀ tán,
19Ìjì ni yóò gbá wọn lọ.