1“Nígbà tí Israẹli wà ní ọmọdé mo fẹ́ràn rẹ̀,
2Bí a ti ń pe wọn,
3Lóòtítọ́ mo kọ́ Efraimu pẹ̀lú ní ìrìn
4Mo fi okùn ènìyàn fà wọ́n
5“Ṣé wọn ò wá ní padà sí Ejibiti bí.
6Idà yóò kọ mọ̀nà ní gbogbo ìlú wọn
7Àwọn ènìyàn mi ti pinnu láti pẹ̀yìndà kúrò lọ́dọ̀ mi
8“Báwo ni èmi ó ṣe fi ọ́ sílẹ̀, Efraimu?
9Èmi kò ni mú ìbínú gbígbóná mi ṣẹ,
10Wọn yóò máa tẹ̀lé Olúwa;
11Wọn ó wá pẹ̀lú ẹ̀rù
12Efraimu tí fi irọ́ yí mi ká