1Efraimu ń jẹ afẹ́fẹ́;
2Olúwa ní ẹjọ́ kan tí yóò bá Juda rò,
3Láti inú oyún ni ó ti di arákùnrin rẹ̀ mú ni gìgísẹ̀,
4Ó bá angẹli ja ìjàkadì, ó sì borí rẹ̀,
5àní Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun;
6Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀;
7Oníṣòwò ń lo òsùwọ̀n èké
8Efraimu gbéraga,
9“Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ;
10Mo sọ fún àwọn wòlíì,
11Gileadi ha burú bí?
12Jakọbu sálọ si orílẹ̀-èdè Aramu;
13Olúwa lo wòlíì kan láti mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti,
14Ṣùgbọ́n Efraimu ti mú un bínú gidigidi;