1Àwọn apanirun ti dìde sí ọ, ìwọ Ninefe.
2Olúwa yóò mú ọláńlá Jakọbu padà sípò
3Asà àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ sì di pupa;
4Àwọn kẹ̀kẹ́ ogun yóò ya bo àwọn pópónà,
5Ninefe yóò ṣe àṣàrò àwọn ọlọ́lá rẹ̀;
6A ó ṣí ìlẹ̀kùn àwọn odò wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀,
7A pa á láṣẹ pé ìlú náà, èyí tí a ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀
8Ninefe dàbí adágún omi,
9“Ẹ kó ìkógun fàdákà!
10Òun ti ṣòfò, ó si di asán, ó sì di ahoro:
11Níbo ni ihò àwọn kìnnìún wà
12Kìnnìún tipa ọ̀pọ̀lọpọ̀ fún àwọn ọmọ rẹ̀,
13“Kíyèsi i èmi dojúkọ ọ́,”