1Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ nípa Ninefe. Ìwé ìran Nahumu ará Elkoṣi.
2Ọlọ́run ń jẹ owú, ó sì ń gbẹ̀san,
3Olúwa lọ́ra láti bínú, ó sì tóbi ní agbára;
4Ó bá òkun wí, ó sì mú kí ó gbẹ;
5Àwọn òkè ńlá wárìrì níwájú rẹ̀,
6Ta ni ó lé dúró níwájú ìbínú rẹ̀?
7Rere ni Olúwa,
8ṣùgbọ́n pẹ̀lú ìkún omi ńlá
9Kí ni ẹ̀yìn ń gbìmọ̀ lòdì sí Olúwa?
10Wọn yóò sì lọ́lù papọ̀ bí ẹ̀gún òṣùṣú
11Láti ọ̀dọ̀ rẹ, ìwọ Ninefe, ni ẹnìkan ti jáde wá
12Báyìí ni Olúwa wí:
13Nísinsin yìí ni èmi yóò já àjàgà wọn kúrò ní ọrùn rẹ
14Olúwa ti fi àṣẹ kan lélẹ̀ nítorí tìrẹ Ninefe:
15Wò ó, lórí àwọn òkè,