1Ègbé ni fún ìlú ẹ̀jẹ̀ nì,
2Ariwo pàṣán àti ariwo
3Ológun orí ẹṣin ń fi ìgbónára
4Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ panṣágà
5“Èmi dojúkọ ọ́,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
6Èmi yóò da ẹ̀gbin tí ó ni ìríra sí ọ ní ara,
7Gbogbo àwọn tí ó ba sì wò ọ́ yóò sì káàánú fún ọ, wọn yóò sì wí pé,
8Ǹjẹ́ ìwọ ha sàn ju Tebesi lọ,
9Etiopia àti Ejibiti ni agbára rẹ, kò sí ní òpin;
10Síbẹ̀síbẹ̀ a kó o ní ìgbèkùn
11Ìwọ pẹ̀lú yóò sì mu àmupara;
12Gbogbo ilé ìṣọ́ agbára rẹ yóò dàbí igi ọ̀pọ̀tọ́
13Kíyèsi gbogbo àwọn jagunjagun!
14Pọn omi nítorí ìhámọ́,
15Níbẹ̀ ni iná yóò ti jó ọ́ run;
16Ìwọ ti sọ àwọn oníṣòwò rẹ di púpọ̀
17Àwọn aládé rẹ̀ dàbí eṣú,
18Ìwọ ọba Asiria,
19Kò sì sí ohun tí ó lè wo ọgbẹ́ ẹ̀ rẹ sàn;