We Believe JesusFé, Esperança e Nova Vida

Nahumu 3

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá

← Nahumu 2 Nahumu

1Ègbé ni fún ìlú ẹ̀jẹ̀ nì,

2Ariwo pàṣán àti ariwo

3Ológun orí ẹṣin ń fi ìgbónára

4Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ panṣágà

5“Èmi dojúkọ ọ́,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.

6Èmi yóò da ẹ̀gbin tí ó ni ìríra sí ọ ní ara,

7Gbogbo àwọn tí ó ba sì wò ọ́ yóò sì káàánú fún ọ, wọn yóò sì wí pé,

8Ǹjẹ́ ìwọ ha sàn ju Tebesi lọ,

9Etiopia àti Ejibiti ni agbára rẹ, kò sí ní òpin;

10Síbẹ̀síbẹ̀ a kó o ní ìgbèkùn

11Ìwọ pẹ̀lú yóò sì mu àmupara;

12Gbogbo ilé ìṣọ́ agbára rẹ yóò dàbí igi ọ̀pọ̀tọ́

13Kíyèsi gbogbo àwọn jagunjagun!

14Pọn omi nítorí ìhámọ́,

15Níbẹ̀ ni iná yóò ti jó ọ́ run;

16Ìwọ ti sọ àwọn oníṣòwò rẹ di púpọ̀

17Àwọn aládé rẹ̀ dàbí eṣú,

18Ìwọ ọba Asiria,

19Kò sì sí ohun tí ó lè wo ọgbẹ́ ẹ̀ rẹ sàn;

← Nahumu 2 Nahumu

Nahumu 3 — iorubá:

Biblica® Open Nkanda wu Moyo, Nguizani Yimona ayi Minkunga 2002