1Nígbà náà, ni mo wí pé,
2Ẹ̀yin tí ó kórìíra ìre, tí ẹ sì fẹ́ràn ibi;
3àwọn tí ó jẹ ẹran-ara àwọn ènìyàn mi,
4Nígbà náà ni wọn yóò kígbe sí Olúwa,
5Báyìí ni Olúwa wí,
6Nítorí náà òru yóò wá sórí yín,
7Ojú yóò sì ti àwọn wòlíì
8Ṣùgbọ́n ní tèmi,
9Gbọ́ ẹ̀yin olórí ilé Jakọbu,
10tí ó kọ́ Sioni pẹ̀lú ìtàjẹ̀ sílẹ̀,
11Àwọn olórí rẹ̀ ń ṣe ìdájọ́ nítorí àbẹ̀tẹ́lẹ̀,
12Nítorí náà, nítorí tiyín,