1Ní ọjọ́ ìkẹyìn
2Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò wá,
3Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ láàrín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn,
4Ṣùgbọ́n olúkúlùkù yóò jókòó lábẹ́ àjàrà rẹ̀
5Gbogbo àwọn ènìyàn ń rìn,
6“Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí,
7Èmi yóò dá àwọn arọ sí fún èyí tókù,
8Ní ti ìwọ, ilé ìṣọ́ agbo àgùntàn,
9Kí ni ìwọ ha ń kígbe sókè sí nísinsin yìí?
10Máa yí síyìn-ín sọ́hùn-ún nínú ìrora,
11Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ọ̀pọ̀lọpọ̀ Orílẹ̀-èdè kó ara wọn jọ sí ọ.
12Ṣùgbọ́n wọn kò mọ
13“Dìde, kí ó sì máa pa ọkà ìwọ ọmọbìnrin Sioni,