1Ègbé ni fún àwọn tí ń gbèrò àìṣedéédéé
2Wọ́n sì ń ṣe ojúkòkòrò oko, wọ́n sì fi agbára wọn gbà wọ́n,
3Nítorí náà, Olúwa wí pé:
4Ní ọjọ́ náà ni ẹnìkan yóò pa òwe kan sí yín;
5Nítorí náà, ìwọ kò ní ní ẹnìkankan tí yóò ta okùn nínú ìjọ Olúwa,
6“Ẹ má ṣe sọtẹ́lẹ̀,” ni àwọn wòlíì wọn wí.
7Ṣé kí á sọ ọ́, ìwọ ilé Jakọbu:
8Láìpẹ́ àwọn ènìyàn mi dìde
9Ẹ̀yin sì lé obìnrin àwọn ènìyàn mi
10Ẹ dìde, kí ẹ sì máa lọ!
11Tí òpùrọ́ àti ẹlẹ́tàn bá wà tí wọ́n sì wí pé,
12“Èmi yóò kó gbogbo yín jọ, ìwọ Jakọbu;
13Ẹni tí ó ń fọ ọ̀nà yóò lọ sókè níwájú wọn;