1Ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Mika ará Moreṣeti wá ní àkókò ìjọba Jotamu, Ahasi, àti Hesekiah, àwọn ọba Juda nìwọ̀nyí, ìran tí ó rí nípa Samaria àti Jerusalẹmu.
2Ẹ gbọ́, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn,
3Wò ó! Olúwa ń bọ̀ wá láti ibùgbé rẹ̀;
4Àwọn òkè ńlá yóò sí yọ́ lábẹ́ rẹ̀,
5Nítorí ìré-òfin-kọjá Jakọbu ni gbogbo èyí,
6“Nítorí náà, èmi yóò ṣe Samaria bí òkìtì lórí pápá,
7Gbogbo àwọn ère fínfín rẹ̀ ni a ó fọ́ sí wẹ́wẹ́
8Nítorí èyí, èmi yóò sì sọkún,
9Nítorí tí ọgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláìlèwòtán;
10Ẹ má ṣe sọ ní Gati
11Ẹ kọjá lọ ni ìhòhò àti ni ìtìjú,
12Nítorí àwọn tí ó ń gbé ni Marati ń retí ìre,
13Ìwọ olùgbé Lakiṣi,
14Nítorí náà ni ìwọ ó ṣe fi ìwé ìkọ̀sílẹ̀
15Èmi yóò sì mú àrólé kan wá sórí rẹ ìwọ olùgbé Meraṣa.
16Fá irun orí rẹ nínú ọ̀fọ̀