1Báwo ni wúrà ṣe sọ ògo dídán rẹ̀ nù,
2Báwo ni àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin Sioni tí ó ṣe iyebíye,
3Àwọn ajáko pèsè ọmú wọn
4Nítorí òǹgbẹ, ahọ́n àwọn ọmọ ọwọ́
5Àwọn tí ó ń jẹ ohun dáradára
6Ìjìyà àwọn ènìyàn mi
7Ọmọ ọba ọkùnrin wọn mọ́ ju òjò-dídì,
8Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n dúdú ju èédú;
9Àwọn tí ó kù nípasẹ̀ idà sàn
10Pẹ̀lú ọwọ́ àwọn obìnrin aláàánú
11Olúwa ti fi ihò kíkún fún ìbínú rẹ̀;
12Àwọn ọba ayé kò gbàgbọ́,
13Èyí ṣẹlẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn wòlíì
14Nísinsin yìí wọ́n ń rìn kiri ní òpópó
15“Lọ kúrò! Ẹ̀yin di aláìmọ́!” ni àwọn ènìyàn ń kígbe sí wọn.
16Olúwa ti tú wọn ká fúnra rẹ̀;
17Síwájú sí i, ojú wa kùnà
18Wọ́n ń ṣọ́ wa kiri,
19Àwọn tí ń lé wa yára
20Ẹni àmì òróró Olúwa, èémí ìyè wa,
21Ẹ yọ̀ kí inú yín sì dùn, ẹ̀yin ọmọbìnrin Edomu,
22Ìwọ ọmọbìnrin Sioni, ìjìyà rẹ yóò dópin;