We Believe JesusFé, Esperança e Nova Vida

Ẹkún Jeremiah 3

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá

← Ẹkún Jeremiah 2 Ẹkún Jeremiah Ẹkún Jeremiah 4 →

1Èmi ni ọkùnrin tí ó rí ìpọ́njú

2Ó ti lé mi jáde ó sì mú mi rìn

3Nítòótọ́, ó ti yí ọwọ́ rẹ̀ padà sí mi

4Ó jẹ́ kí àwọ̀ mi àti ẹran-ara mi gbó

5Ó ti fi mí sí ìgbèkùn, ó sì ti yí mi ká

6Ó mú mi gbé nínú òkùnkùn,

7Ó ti tì mí mọ́ ilé, nítorí náà n kò le è sálọ;

8Pàápàá nígbà tí mo ké fún ìrànlọ́wọ́,

9Ó fi ògiri òkúta dí ọ̀nà mi;

10Bí i beari tí ó dùbúlẹ̀,

11Ó wọ́ mi kúrò ní ọ̀nà, ó tẹ̀ mí mọ́lẹ̀

12Ó fa ọfà rẹ̀ yọ

13Ó fa ọkàn mí ya

14Mo di ẹni yẹ̀yẹ́ láàrín àwọn ènìyàn mi;

15Ó ti kún mi pẹ̀lú ewé kíkorò

16Ó ti fi òkúta kán eyín mi;

17Mo ti jìnnà sí àlàáfíà;

18Nítorí náà mo wí pé, “Ògo mi ti lọ

19Mo ṣe ìrántí ìpọ́njú àti ìdààmú mi,

20Mo ṣèrántí wọn,

21Síbẹ̀, èyí ni mo ní ní ọkàn

22Nítorí ìfẹ́ Olúwa tí ó lágbára ni àwa kò fi ṣègbé,

23Wọ́n jẹ́ ọ̀tún ní àárọ̀;

24Mo wí fún ara mi, ìpín mi ni Olúwa;

25Dídára ni Olúwa fún àwọn tí ó ní ìrètí nínú rẹ̀,

26Ó dára kí a ní sùúrù

27Ó dára fún ènìyàn láti gbé àjàgà

28Jẹ́ kí ó jókòó ní ìdákẹ́ jẹ́ẹ́,

29Jẹ́ kí ó bo ojú rẹ̀ sínú eruku—

30Jẹ́ kí ó fi ẹ̀rẹ̀kẹ́ fún àwọn tí yóò gbá a,

31Ènìyàn kò di ìtanù

32Lóòtítọ́ ó mú ìbànújẹ́ wá, yóò fi àánú hàn,

33Nítorí kò mọ̀ ọ́n mọ̀ mú ìpọ́njú wá

34Láti tẹ mọ́lẹ̀ lábẹ́ ẹsẹ̀

35Láti ṣẹ́ ọmọ ènìyàn fún ẹ̀tọ́ rẹ̀

36láti yí ìdájọ́ ènìyàn padà,

37Ta ni yóò sọ̀rọ̀ tí yóò rí bẹ́ẹ̀

38Ǹjẹ́ kì í ṣe láti ẹnu Ọ̀gá-ògo jùlọ

39Kí ló dé tí ẹ̀dá alààyè ṣe ń kùn

40Ẹ jẹ́ kí a yẹ ọ̀nà wa, kí a sì dán an wò,

41Ẹ jẹ́ kí a gbé ọkàn àti ọwọ́ wa sókè

42“Àwa ti ṣẹ̀ a sì ti ṣọ̀tẹ̀

43“Ìwọ fi ìbínú bo ara rẹ ìwọ sì ń lépa wa;

44Ìwọ ti fi àwọsánmọ̀ bo ara rẹ

45Ó ti sọ wá di èérí àti ààtàn

46“Gbogbo àwọn ọ̀tá wa ti la ẹnu wọn

47Àwa ti jìyà àti ìparun,

48Omijé ń sàn ní ojú mi bí odò

49Ojú mi kò dá fún omijé,

50títí ìgbà tí Olúwa yóò síjú wolẹ̀

51Ohun tí mo rí mú ìbẹ̀rù wá ọkàn mi

52Àwọn tí ó jẹ́ ọ̀tá mi láìnídìí

53Wọ́n gbìyànjú láti mú òpin dé bá ayé mi nínú ihò

54Orí mi kún fún omi,

55Mo pe orúkọ rẹ, Olúwa,

56Ìwọ gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi, “Má ṣe di etí rẹ

57O wá tòsí nígbà tí mo ké pè ọ́,

58Olúwa, ìwọ gba ẹjọ́ mi rò,

59O ti rí i, Olúwa, búburú tí a ṣe sí mi.

60Ìwọ ti rí ọ̀gbun ẹ̀san wọn,

61Olúwa ìwọ ti gbọ́ ẹ̀gàn wọn

62ohun tí àwọn ọ̀tá mi ń sọ

63Wò wọ́n! Ní jíjòkòó tàbí ní dídìde,

64Olúwa san wọ́n lẹ́san ohun tí ó tọ́ sí wọn

65Fi ìbòjú bò wọ́n ní ọkàn,

66Ni wọ́n lára kí o sì pa wọ́n run pẹ̀lú ìbínú,

← Ẹkún Jeremiah 2 Ẹkún Jeremiah Ẹkún Jeremiah 4 →

Ẹkún Jeremiah 3 — iorubá:

Biblica® Open Nkanda wu Moyo, Nguizani Yimona ayi Minkunga 2002