1Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa fi sẹ́nu wòlíì Jeremiah láti sọ fún ará ilẹ̀ Babeli:
2“Ẹ sọ ọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ẹ sì kéde,
3Àwọn ìlú ní apá àríwá yóò
4“Ní ọjọ́ wọ̀nyí àti ní àkókò náà,”
5Wọn ó máa béèrè ọ̀nà Sioni,
6“Àwọn ènìyàn mi ti jẹ́ àgùntàn tí ó sọnù,
7Gbogbo àwọn tí ó rí wọn, ti pa wọ́n jẹ
8“Jáde kúrò ní Babeli,
9Nítorí pé èmi yóò ru,
10A ó dààmú Babeli,
11“Nítorí pé inú yín dùn nítorí pé ẹ̀yìn yọ̀,
12Ojú yóò ti ìyá rẹ, ẹni tí ó bí ọ
13Nítorí ìbínú Olúwa, kì yóò ní olùgbé;
14“Dúró sí ààyè rẹ ìwọ Babeli
15Kígbe mọ́ ọn ní gbogbo ọ̀nà!
16Ké afúnrúgbìn kúrò ní Babeli,
17“Israẹli jẹ́ àgùntàn tí ó ṣìnà kiri,
18Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Alágbára, Ọlọ́run Israẹli wí,
19Ṣùgbọ́n, èmi yóò mú Israẹli
20Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,”
21“Kọlu ilẹ̀ Merataimu àti àwọn
22Ariwo ogun wà ní ilẹ̀ náà
23Báwo ni ó ṣe fọ́, tí ó sì pín yẹ́lẹyẹ̀lẹ tó,
24Mo dẹ pàkúté sílẹ̀
25Olúwa ti kó àwọn ohun èlò ìjà rẹ̀ jáde,
26Ẹ wá sórí rẹ̀ láti òpin gbogbo,
27Pa gbogbo àwọn akọ màlúù rẹ,
28Gbọ́ ohùn àwọn tí ó sálọ, tí ó sì sálà láti Babeli wá,
29“Pe ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àní gbogbo tafàtafà, sórí Babeli,
30Nítorí náà, àwọn ọmọkùnrin rẹ̀
31“Wò ó, èmi yóò dojú kọ ọ́ ìwọ agbéraga,”
32Onígbèéraga yóò kọsẹ̀, yóò sì ṣubú,
33Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ:
34Síbẹ̀, Olùràpadà wọn, Alágbára,
35“Idà lórí àwọn Babeli!”
36Idà lórí àwọn wòlíì èké
37Idà lórí àwọn kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀
38Ilẹ̀ gbígbẹ lórí omi rẹ̀; yóò sì gbẹ.
39“Nítorí náà àwọn ẹranko ijù
40Gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti gba ìjọba Sodomu àti Gomorra
41“Wò ó! Ọ̀wọ́ ọmọ-ogun láti ìhà àríwá;
42Wọ́n sì di ìhámọ́ra ọ̀kọ̀ àti ọrun,
43Ọba Babeli ti gbọ́ ìròyìn nípa wọn,
44Bí i kìnnìún ni òun ó gòkè wá láti igbó Jordani
45Nítorí náà, gbọ́ ohun tí
46Ní ohùn igbe ńlá pé;