1Nípa Moabu.
2Moabu kò ní ní ìyìn mọ́,
3Gbọ́ igbe ní Horonaimu,
4Moabu yóò di wíwó palẹ̀;
5Wọ́n gòkè lọ sí Luhiti,
6Sá! Àsálà fún ẹ̀mí yín;
7Níwọ́n ìgbà tí o gbẹ́kẹ̀lé agbára àti ọrọ̀ rẹ,
8Gbogbo ìlú rẹ ni apanirun yóò dojúkọ,
9Fi iyọ̀ sí Moabu,
10“Ìfibú ni fún ẹni tí ó fi ìmẹ́lẹ́ ṣe iṣẹ́ Olúwa,
11“Moabu ti wà ní ìsinmi láti ìgbà èwe rẹ̀ wá
12Ṣùgbọ́n ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí,
13Nígbà náà Moabu yóò sì tú u nítorí Kemoṣi,
14“Báwo ni o ṣe lè sọ pé, ‘Ajagun ni wá,
15A ó pa Moabu run, a ó sì gba àwọn ìlú rẹ̀;
16“Ìṣubú Moabu súnmọ́;
17Ẹ dárò fún, gbogbo ẹ̀yin tí ó yí i ká
18“Sọ̀kalẹ̀ níbi ògo rẹ,
19Dúró lẹ́bàá ọ̀nà kí o sì wòran,
20Ojú ti Moabu nítorí tí a wó o lulẹ̀.
21Ìdájọ́ ti dé sí àwọn òkè pẹrẹsẹ,
22sórí Diboni, Nebo àti Beti-Diblataimu,
23sórí Kiriataimu, Beti-Gamu àti Beti-Meoni,
24sórí Kerioti àti Bosra,
25A gé ìwo Moabu kúrò,
26“Ẹ jẹ́ kí a mú u mutí
27Ǹjẹ́ Israẹli kò di ẹni ẹ̀gàn rẹ?
28Kúrò ní àwọn ìlú rẹ, kí o sì máa gbé láàrín àwọn òkúta,
29“A ti gbọ́ nípa ìgbéraga Moabu:
30Mo mọ àfojúdi rẹ̀, ṣùgbọ́n òfo ni,” ni Olúwa wí,
31Nítorí náà, mo pohùnréré ẹkún lórí Moabu
32Mo sọkún fún ọ bí Jaseri ṣe sọkún
33Ayọ̀ àti ìdùnnú ti kúrò
34“Ohùn igbe wọn gòkè
35Ní ti Moabu ni èmi yóò ti fi òpin sí
36“Nítorí náà ọkàn mi ró fún Moabu bí fèrè,
37Gbogbo orí ni yóò pá,
38Ẹkún ńlá ní yóò wà lórí gbogbo òrùlé Moabu,
39“Èéṣe tí ẹ fi fọ́ túútúú,
40Báyìí ni Olúwa wí:
41Kerioti ni a ó kó lẹ́rú àti ilé agbára ni ó gbà.
42A ó pa Moabu run gẹ́gẹ́ bí
43Ẹ̀rù àti ọ̀fìn àti okùn dídè
44“Ẹnikẹ́ni tí ó bá sá fún
45“Ní abẹ́ òjìji Heṣboni
46Ègbé ní fún ọ Moabu!
47“Síbẹ̀, èmi yóò dá ìkólọ