1Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tó tọ wòlíì Jeremiah wá nípa àwọn Filistini, kí ó tó di pé Farao dojúkọ Gasa.
2Báyìí ni Olúwa wí:
3nígbà tí wọ́n bá gbọ́ ìró títẹ̀lé pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin alágbára
4Nítorí tí ọjọ́ náà ti pé
5Gasa yóò fá irun orí rẹ̀ nínú ọ̀fọ̀.
6“Ẹ̀yin kígbe, ‘Yé è, idà Olúwa,
7Ṣùgbọ́n báwo ni yóò ṣe sinmi,