1Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Jeremiah wòlíì wá nípa àwọn Orílẹ̀-èdè.
2Nípa Ejibiti.
3“Ẹ múra àpáta, èyí tí ó tóbi, àti èyí tí ó kéré,
4Ẹ di ẹṣin ní gàárì,
5Kí ni nǹkan tí mo tún rí?
6“Ẹni tí ó yára kì yóò le sálọ,
7“Ta ni èyí tí ó gòkè wá bí odò Ejibiti,
8Ejibiti dìde bí odò náà,
9Ẹ gòkè wá ẹ̀yin ẹṣin,
10Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà jẹ́ ti Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,
11“Gòkè lọ sí Gileadi, kí o sì mú ìkunra,
12Àwọn orílẹ̀-èdè yóò gbọ́ nípa ìtìjú rẹ,
13Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó bá Jeremiah wòlíì nì sọ nípa wíwá Nebukadnessari ọba Babeli láti lọ dojú ìjà kọ Ejibiti:
14“Kéde èyí ní Ejibiti, sì sọ ọ́ ní Migdoli,
15Èéṣe tí àwọn akọni rẹ fi ṣubú?
16Wọn yóò máa ṣubú léraléra
17Níbẹ̀ ni wọn ó kígbe pé,
18“Bí èmi ti wà láààyè,” ni ọba,
19Ìwọ, ọmọbìnrin ti ń gbé Ejibiti
20“Ẹgbọrọ abo màlúù tó lẹ́wà ní Ejibiti
21Àwọn jagunjagun rẹ̀
22Ejibiti yóò pòṣé bí ejò tí ń sá
23Wọn o gé igbó rẹ̀ lulẹ̀,” ni Olúwa wí,
24A ó dójútì ọmọbìnrin Ejibiti,
25Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí pé: “Èmi yóò rọ̀jò ìyà mi sórí Amoni òrìṣà Tebesi, sórí Farao, sórí Ejibiti àti àwọn òrìṣà rẹ̀ àti sórí àwọn ọba rẹ̀ àti sórí àwọn tó gbẹ́kẹ̀lé Farao.
26Èmi ó sì fi wọ́n lé àwọn tó wá ẹ̀mí wọn lọ́wọ́, lé Nebukadnessari ọba Babeli, ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, Ejibiti yóò sì di gbígbé bí i ti àtijọ́,” ni Olúwa wí.
27“Má bẹ̀rù, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi,
28Má bẹ̀rù, Jakọbu ìránṣẹ́ mi,