1Olúwa yóò fi àánú hàn fún Jakọbu,
2Àwọn orílẹ̀-èdè yóò gbà wọ́n
3Ní ọjọ́ tí Olúwa yóò fi ìtura fún un yín kúrò nínú ìpọ́njú àti ìyà àti ìdè ìkà,
4ẹ ó sì fi ọ̀rọ̀ àbùkù yìí kan ọba Babeli pé,
5Olúwa ti dá ọ̀pá ìkà náà,
6èyí tí ó ti lu àwọn ènìyàn bolẹ̀
7Gbogbo ilẹ̀ ni ó wà ní ìsinmi àti àlàáfíà,
8Pẹ̀lúpẹ̀lú àwọn igi junifa àti àwọn
9Ibojì tí ó wà ní ìsàlẹ̀ ni a ru sókè
10Gbogbo wọn yóò dáhùn,
11Gbogbo rẹ̀ ni ó di ìrẹ̀sílẹ̀ lọ sí ibojì,
12Báwo ni ìwọ ṣe ṣubú lulẹ̀ láti ọ̀run wá,
13Ìwọ sọ nínú ọkàn rẹ pé,
14Èmi yóò gòkè lọ rékọjá àwọn àwọsánmọ̀;
15Ṣùgbọ́n a ti rẹ̀ ọ́ sílẹ̀ wọ inú ibojì lọ
16Àwọn tí ó rí ọ yóò tẹjúmọ́ ọ,
17Ẹni tí ó sọ ayé di aginjù,
18Gbogbo àwọn ọba orílẹ̀-èdè ni a tẹ́ sílẹ̀
19Ṣùgbọ́n a jù ọ́ síta kúrò nínú ibojì
20a kò ní sin ọ́ pẹ̀lú wọn,
21Tọ́jú ibìkan tí a ó ti pa àwọn ọmọkùnrin rẹ
22“Èmi yóò dìde sókè sí wọn,”
23Èmi yóò yí i padà sí ibùgbé àwọn òwìwí
24Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti búra,
25Èmi yóò run Asiria ní ilẹ̀ mi,
26Èyí ni ètò tí a pinnu rẹ̀ fún gbogbo ayé,
27Nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti pète,
28Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ yí wá ní ọdún tí ọba Ahasi kú.
29Má ṣe yọ̀, gbogbo ẹ̀yin Filistia,
30Ẹni tí ó kúṣẹ̀ẹ́ jù yóò ní pápá oko,
31Hu, ìwọ ẹnu-ọ̀nà! Kígbe, ìwọ ìlú!
32Kí ni ìdáhùn tí a ó fún