1Gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ìwọ ilé Israẹli, ìpohùnréré ẹkún tí mo ṣe nípa rẹ:
2“Wúńdíá Israẹli ṣubú
3Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí:
4Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún ilé Israẹli:
5ẹ má ṣe wá Beteli,
6Ẹ wá Olúwa, ẹ̀yin yóò sì yè,
7Ẹ̀yin tí ẹ̀ sọ òdodo di ìkorò
8Ẹni tí ó dá ìràwọ̀ Pleiadesi àti Orioni
9Ó fọ́n ìparun sí ìlú olódi
10Ìwọ kórìíra ẹni tí ń bá ni wí ní ẹnu ibodè
11Ìwọ ń tẹ tálákà mọ́lẹ̀
12Nítorí mo mọ iye àìṣedéédéé rẹ
13Àwọn ọlọ́gbọ́n máa ń dákẹ́ jẹ́ẹ́ ní àkókò wọ̀nyí,
14Wá rere, má ṣe wá búburú
15Kórìíra búburú kí o sì fẹ́ rere
16Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun wí:
17Ìpohùnréré ẹkún yóò wà ní gbogbo ọgbà àjàrà,
18Ègbé ni fún ìwọ tí ó pẹ́
19Gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí ó sá fún kìnnìún,
20Ǹjẹ́ ọjọ́ Olúwa kò ha ní ṣókùnkùn dípò kí ó ní ìmọ́lẹ̀?
21“Mo kórìíra, mo kẹ́gàn àwọn àsè ẹ̀sìn in yín,
22Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ mú ẹbọ sísun àti ọrẹ ọkà wá.
23Ẹ gbé ariwo orin yín sẹ́yìn!
24Jẹ́ kí òtítọ́ sàn bí odò
25“Àbí ẹ̀yin mú ẹbọ àti ọrẹ tọ̀ mí wá
26Ẹ̀yin ti gbé ibi ìrúbọ àwọn ọba yín sókè,
27Nítorí náà èmi yóò rán an yín lọ sí ìgbèkùn ní ìkọjá Damasku,”