1Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ẹ̀yin màlúù Baṣani lórí òkè Samaria,
2Olúwa Olódùmarè ti fi ìwà mímọ́ rẹ̀ búra:
3Ẹni kọ̀ọ̀kan yín yóò jáde lọ
4“Ẹ lọ sí Beteli láti dẹ́ṣẹ̀;
5Kí ẹ mú ọ̀rẹ́ ìdúpẹ́ ìyẹ̀fun ìwúkàrà ti a sun
6“Èmi fún un yín ní mímọ́ eyín ní gbogbo ìlú yín,
7“Àti pẹ̀lú mo mú òjò dúró
8Àwọn ènìyàn ń rìn láti ìlú kan sí ìlú mìíràn fún omi
9“Lọ́pọ̀ ìgbà ni mo kọlu ọgbà àti ọgbà àjàrà yín
10“Mo rán àjàkálẹ̀-ààrùn sí i yín
11“Mo ti bì ṣubú nínú yín,
12“Nítorí náà, èyí ni ohun tí èmi yóò ṣe sí i yín, Israẹli,
13Ẹni tí ó dá àwọn òkè