1Èyí ni ohun tí Olúwa wí,
2Èmi yóò rán iná sí orí Moabu
3Èmi yóò ké onídàájọ́ rẹ̀ kúrò,
4Èyí ni ohun tí Olúwa wí,
5Èmi yóò rán iná sí orí Juda
6Èyí ni ohun tí Olúwa wí:
7Wọ́n fi ẹsẹ̀ tẹ orí àwọn tálákà mọ́lẹ̀,
8Wọ́n dùbúlẹ̀ lẹ́bàá a pẹpẹ,
9“Mo pa àwọn ará Amori run níwájú wọn
10Èmi mú un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá,
11“Èmi sì tún gbé àwọn wòlíì dìde láàrín àwọn ọmọ yín
12“Ṣùgbọ́n ẹ̀yin fún àwọn Nasiri ní ọtí mu
13“Ní báyìí, èmi yóò tẹ̀ yín mọ́lẹ̀
14Ẹni tí ó yára bí àṣá kò ní rí ọ̀nà àbáyọ
15Tafàtafà kì yóò dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ̀
16Àní jagunjagun tí ó gbóyà jùlọ