1Olúwa jẹ ọba;
2Olúwa tóbi ní Sioni;
3Kí wọ́n sì yin orúkọ rẹ̀ tí ó tóbi
4Ọba náà ní agbára, ó sì fẹ́ òdodo,
5Gbígbéga ni Olúwa Ọlọ́run wa
6Mose àti Aaroni wà nínú àwọn àlùfáà rẹ̀
7Ó sọ̀rọ̀ sí wọn nínú ọ̀wọ́n àwọsánmọ̀,
8Olúwa Ọlọ́run wa, ó dá wọn lóhùn;
9Gbígbéga ni Olúwa Ọlọ́run wa