1Ẹ kọrin tuntun sí Olúwa,
2Olúwa ti sọ ìgbàlà rẹ̀ di mí mọ̀
3Ó rántí ìfẹ́ rẹ̀ àti òtítọ́ rẹ̀ fún àwọn ará ilé Israẹli;
4Ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Olúwa, gbogbo ayé,
5ẹ fi dùùrù kọrin sí Olúwa, pẹ̀lú dùùrù àti ìró ohùn orin mímọ́,
6pẹ̀lú ìpè àti fèrè
7Jẹ́ kí òkun kí ó hó pẹ̀lú gbogbo
8Ẹ jẹ́ kí odo kí ó ṣápẹ́,
9ẹ jẹ́ kí wọn kọrin níwájú Olúwa,