1Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
2Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni
3Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀,
4“Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli
5Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ,
6Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀:
7Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá
1Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
2Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni
3Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀,
4“Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli
5Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ,
6Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀:
7Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu