1Ọlọ́run, àwọn orílẹ̀-èdè ti wá ilẹ̀ ìní rẹ;
2Wọn ti fi ara òkú àwọn ìránṣẹ́ rẹ
3Wọ́n tu ẹ̀jẹ̀ jáde gẹ́gẹ́ bí omi
4Àwa di ohun ẹ̀gàn sí àwọn tí ó yí wa ká,
5Nígbà wo, Olúwa? Ní ìwọ ó máa bínú títí láé?
6Tú ìbínú rẹ jáde sí orílẹ̀-èdè
7nítorí wọ́n ti run Jakọbu
8Má ṣe ka ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba wa sí wa lọ́rùn
9Ràn wá lọ́wọ́, Ọlọ́run Olùgbàlà wa,
10Àwọn orílẹ̀-èdè yóò máa wí pé,
11Jẹ́ kí ìmí ẹ̀dùn oǹdè náà wá síwájú rẹ,
12San án padà sí àyà àwọn aládùúgbò wa nígbà méje
13Nígbà náà àwa ènìyàn rẹ,