1Olúwa Ọlọ́run mi, ààbò mi wà nínú rẹ;
2kí wọn ó má ba à fa ọkàn mi ya gẹ́gẹ́ bí kìnnìún,
3Olúwa Ọlọ́run mi, tí èmi bá ṣe èyí
4bí èmi bá ṣe ibi sí ẹni tí ń wá àlàáfíà pẹ̀lú mi,
5nígbà náà, jẹ́ kí ọ̀tá mi lé mi kí wọn sì mú mi;
6Dìde, Olúwa, nínú ìbínú rẹ;
7Kí ìpéjọ àwọn ènìyàn yíká.
8Jẹ́ kí Olúwa ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn.
9Ọlọ́run Olódodo,
10Ààbò mi ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run,
11Ọlọ́run ni onídàájọ́ òtítọ́,
12Bí kò bá yípadà,
13Ó ti pèsè ohun ìjà ikú sílẹ̀;
14Ẹni tí ó lóyún ohun búburú,
15Ẹni tí ó gbẹ́ ọ̀fìn, tí ó kó o jáde
16Wàhálà tí ó fà padà sórí rẹ̀;
17Èmi ó fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí òdodo rẹ̀,