1Olúwa, má ṣe bá mi wí nínú ìbínú rẹ
2Ṣàánú fún mi, Olúwa, nítorí èmi ń kú lọ;
3Ọkàn mi wà nínú ìrora.
4Yípadà, Olúwa, kí o sì gbà mí;
5Ẹnikẹ́ni kò ni rántí rẹ nígbà tí ó bá kú.
6Agara ìkérora mi dá mi tán.
7Ojú mi di aláìlera pẹ̀lú ìbànújẹ́;
8Kúrò lọ́dọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin tí ń ṣe iṣẹ́ ibi,
9Olúwa ti gbọ́ ẹkún mi fún àánú;
10Gbogbo àwọn ọ̀tá mi lójú yóò tì, wọn yóò sì dààmú;