1Mo wí pé, “Èmi yóò ṣọ́ ọ̀nà mi
2Mo fi ìdákẹ́ ya odi;
3Àyà mi gbóná ní inú mi.
4“Olúwa, jẹ́ kí èmi kí ó mọ òpin mi,
5Ìwọ ti ṣe ayé mi
6“Nítòótọ́ ni olúkúlùkù ń rìn kiri bí òjìji.
7“Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí,
8Gbà mí lọ́wọ́ ìrékọjá mi gbogbo.
9Mo dákẹ́ jẹ́ẹ́;
10Mú pàṣán rẹ kúrò ní ara mi;
11Ìwọ fi ìbáwí kìlọ̀
12“Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa,
13Dá mi sí, kí èmi lè ní agbára,