We Believe JesusFé, Esperança e Nova Vida

Saamu 35

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá

← Saamu 34 Saamu Saamu 36 →

1Olúwa, gbógun ti àwọn tí ń gbóguntì mí;

2Di asà àti àpáta mú,

3Fa idà àti ọ̀kọ̀ yọ

4Kí wọn kí ó dààmú,

5Jẹ́ kí wọn dàbí ìyàngbò níwájú afẹ́fẹ́,

6Jẹ́ kí ọ̀nà wọn kí ó ṣókùnkùn, kí ó sì máa yọ́,

7Nítorí pé, ní àìnídìí ni wọ́n dẹ àwọ̀n wọn sílẹ̀ fún mi,

8Kí ìparun kí ó wá sí orí rẹ̀ ní òjijì.

9Nígbà náà ni ọkàn mi yóò yọ̀ nínú Olúwa,

10Gbogbo egungun mi yóò wí pé,

11Àwọn ẹlẹ́rìí èké dìde;

12Wọ́n fi búburú san ìre fún mi;

13Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti èmi ni, nígbà tí wọn ń ṣe àìsàn, mo wọ aṣọ ọ̀fọ̀;

14èmí ń lọ kiri bí ẹni ń ṣọ̀fọ̀

15Ṣùgbọ́n nínú ìkọ̀sẹ̀ mi wọ́n sì yọ̀, wọ́n sì kó ara wọn jọ;

16Bí àwọn àgàbàgebè tí ń ṣe ẹlẹ́yà ní àpèjẹ

17Yóò ti pẹ́ tó Olúwa, tí ìwọ yóò máa wò wọ́n lọ?

18Nígbà náà ni èmi yóò ṣọpẹ́ fún Ọ nínú àjọ ńlá;

19Má ṣe jẹ́ kí àwọn ọ̀tá mi

20Nítorí pé wọn kò sọ ọ̀rọ̀ àlàáfíà,

21Wọ́n ya ẹnu wọn gbòòrò sí mi; wọ́n wí pé, “Háà! Háà!

22Ìwọ́ ti rí i Olúwa; má ṣe dákẹ́!

23Dìde! ru ara rẹ̀ sókè fún ààbò mi,

24Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa Ọlọ́run mi, gẹ́gẹ́ bí òdodo rẹ,

25Má ṣe jẹ́ kí wọn wí nínú ara wọn pé, “Háà! A ti rí ohun tí ọkàn wa ń fẹ́!”

26Kí ojú kí ó tì wọ́n,

27Jẹ́ kí àwọn tí ó fẹ́ ìdáláre mi

28Nígbà náà ni ahọ́n mi yóò máa sọ̀rọ̀ òdodo rẹ,

← Saamu 34 Saamu Saamu 36 →

Saamu 35 — iorubá:

Biblica® Open Nkanda wu Moyo, Nguizani Yimona ayi Minkunga 2002