1Ìbùkún ni fún àwọn
2Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà
3Nígbà tí mo dákẹ́,
4Nítorí pé ni ọ̀sán àti ní òru
5Èmi jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi sí ọ
6Nítorí náà jẹ́ kí gbogbo àwọn olódodo máa gbà àdúrà sí ọ
7Ìwọ ni ibi ìpamọ́ mi;
8Èmi yóò kọ́ ọ, èmi yóò sì fi ẹsẹ̀ rẹ lé ọ̀nà tí ìwọ yóò rìn
9Má ṣe dàbí ẹṣin tàbí ìbáaka,
10Ọ̀pọ̀ ìkáàánú ní yóò wà fún ènìyàn búburú,
11Ẹ yọ̀ nínú Olúwa, kí ẹ sì ní inú dídùn, ẹ̀yìn olódodo;