1Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa,
2Wádìí mi wò, Ìwọ Olúwa, kí o sì dán mi wò,
3nítorí ìfẹ́ ẹ̀ rẹ tí ó dúró ṣinṣin ń bẹ níwájú mi,
4Èmi kò jókòó pẹ̀lú aláìṣòótọ́,
5Èmi ti kórìíra àwùjọ àwọn ènìyàn búburú
6Èmí ó wẹ ọwọ́ mi ní àìlẹ́ṣẹ̀,
7Èmi yóò kọrin sókè àní orin ọpẹ́,
8Háà Olúwa, èmí ń fẹ́ ilé rẹ níbi tí ìwọ ń gbé,
9Má ṣe gbá mi dànù pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,
10àwọn tí ọwọ́ wọn kún fún ìwà ibi,
11Ṣùgbọ́n èmi ó máa rìn nínú ìwà títọ́;
12Ẹsẹ̀ mi dúró lórí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú;