1Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
2Ẹ yìn ín fún iṣẹ́ agbára rẹ̀.
3Ẹ fi ohùn ìpè yìn ín.
4Ẹ fi ohun èlò orin àti ijó yìn ín
5Ẹ yìn ín pẹ̀lú aro olóhùn òkè,
6Jẹ́ kí gbogbo ohun tí ó ní ẹ̀mí yin Olúwa.
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá
1Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
2Ẹ yìn ín fún iṣẹ́ agbára rẹ̀.
3Ẹ fi ohùn ìpè yìn ín.
4Ẹ fi ohun èlò orin àti ijó yìn ín
5Ẹ yìn ín pẹ̀lú aro olóhùn òkè,
6Jẹ́ kí gbogbo ohun tí ó ní ẹ̀mí yin Olúwa.