1Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
2Jẹ́ kí Israẹli kí ó ní inú dídùn sí ẹni tí ó dá a
3Jẹ́ kí wọn kí ó fi ijó yin orúkọ rẹ̀
4Nítorí Olúwa ní inú dídùn sí àwọn ènìyàn rẹ̀
5Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mímọ́ kí ó yọ̀ nínú ọlá rẹ̀
6Kí ìyìn Ọlọ́run kí ó wà ní ẹnu wọn
7Láti gba ẹ̀san lára àwọn orílẹ̀-èdè,
8láti fi ẹ̀wọ̀n de àwọn ọba wọn
9Láti ṣe ìdájọ́ tí àkọsílẹ̀ rẹ̀ sí wọn