1Ìyìn sí Olúwa àpáta mi,
2Òun ni Ọlọ́run ìfẹ́ mi àti odi alágbára mi,
3Olúwa, kí ni ènìyàn tí ìwọ fi ń ṣàníyàn fún un,
4Ènìyàn rí bí èmi;
5Tẹ ọ̀run rẹ ba, Olúwa, kí o sì sọ̀kalẹ̀;
6Rán mọ̀nàmọ́ná kí ó sì fọ́n àwọn ọ̀tá ká;
7Na ọwọ́ rẹ sílẹ̀ láti ibi gíga;
8Ẹnu ẹni tí ó kún fún èké
9Èmi yóò kọ orin tuntun sí ọ
10Òun ni ó fi ìgbàlà fún àwọn ọba,
11Gbà mí kí o sì yọ mí nínú ewu
12Kí àwọn ọmọkùnrin wa
13Àká wa yóò kún
14àwọn màlúù wa yóò ru ẹrù wúwo
15Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn náà tí ó wà ní irú ipò bẹ́ẹ̀,