1Olúwa gbọ́ àdúrà mi,
2Má ṣe mú ìránṣẹ́ rẹ wá sí ìdájọ́,
3Ọ̀tá ń lépa mi,
4Nítorí náà ẹ̀mí mi ṣe rẹ̀wẹ̀sì nínú mi;
5Èmi rántí ọjọ́ tí ó ti pẹ́;
6Èmi na ọwọ́ mi jáde sí ọ:
7Dá mi lóhùn kánkán, Olúwa;
8Mú mi gbọ́ ìṣeun ìfẹ́ rẹ ní òwúrọ̀:
9Gbà mí kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi, Olúwa,
10Kọ́ mi láti ṣe ìfẹ́ rẹ,
11Nítorí orúkọ rẹ, Olúwa, sọ mi di ààyè;
12Nínú ìfẹ́ rẹ tí kì í kùnà, ké àwọn ọ̀tá mi kúrò,