1Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó ṣeun;
2Jẹ́ kí àwọn ẹni ìràpadà Olúwa kí ó wí báyìí,
3àwọn tí ó kójọ láti ilẹ̀ wọ̀n-ọn-nì,
4Wọ́n ń rìn káàkiri ní aginjù ní ibi tí ọ̀nà kò sí,
5Ebi ń pa wọn, òǹgbẹ gbẹ wọ́n,
6Ní ìgbà náà, wọ́n kígbe sókè
7Ó fi ọ̀nà títọ́ hàn wọ́n sí ìlú
8Ẹ jẹ́ kí wọn máa yin Olúwa nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti nítorí iṣẹ́
9nítorí tí ó tẹ́ ìfẹ́ ọkàn lọ́run
10Ọ̀pọ̀ jókòó nínú òkùnkùn àti òjìji ikú,
11nítorí tí wọ́n ṣe àìgbọ́ràn sí ọ̀rọ̀
12Ó sì fi ìkorò rẹ àyà wọn sílẹ̀;
13Ní ìgbà náà wọ́n ké pe
14Ó mú wọn jáde kúrò nínú
15Ẹ jẹ́ kí wọn fi ọpẹ́ fún Olúwa! Nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti nítorí iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ sí ọmọ ènìyàn.
16Nítorí tí ó já ìlẹ̀kùn idẹ wọ̀n-ọn-nì
17Ọ̀pọ̀ di aṣiwèrè nítorí ìrékọjá wọn
18Wọ́n kọ gbogbo oúnjẹ
19Nígbà náà wọ́n kígbe sí Olúwa nínú ìṣòro wọn,
20Ó rán ọ̀rọ̀ rẹ̀, ara wọn sì dá
21Ẹ jẹ́ kí wọ́n fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ fún ọmọ ènìyàn.
22Jẹ́ kí wọn rú ẹbọ ọpẹ́
23Àwọn tí ń sọ̀kalẹ̀ lọ sí Òkun nínú ọkọ̀ ojú omi,
24Wọ́n rí iṣẹ́ Olúwa,
25Nítorí tí ó pàṣẹ, ó sì mú ìjì fẹ́
26Wọ́n gòkè lọ sí ọ̀run wọ́n sì
27Wọ́n ń ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n bí ọ̀mùtí ènìyàn:
28Nígbà náà wọ́n ń kígbe sókè
29Ó sọ ìjì di ìdákẹ́rọ́rọ́
30Inú wọn dùn nígbà tí ara wọn balẹ̀,
31Jẹ́ kí wọn fi ọpẹ́ fún
32Jẹ́ kí wọn gbé e ga ní àárín àwọn ènìyàn
33Ó sọ odò di aginjù,
34Ilẹ̀ eléso di aṣálẹ̀
35O sọ aginjù di adágún omi àti
36níbẹ̀ ó mú ẹni tí ebi ń pa wà,
37Wọn fún irúgbìn, wọ́n sì gbin ọgbà àjàrà
38Ó bùkún wọn, wọ́n sì pọ̀ sí i ní iye
39Nígbà náà, ọjọ́ wọn kúrú,
40ẹni tí ó da ẹ̀gàn lu ọmọ-aládé
41Ṣùgbọ́n ó gbé aláìní sókè kúrò nínú ìnira
42Àwọn tí ó dúró sì rí i, inú wọn sì dùn
43Ẹni tí ó bá gbọ́n, jẹ́ kí ó kíyèsi nǹkan wọ̀nyí